Segun Awolowo | |
---|---|
![]() | |
Ààrẹ National Trade Promotion Organisation | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
Ó gun orí àga 2021 | |
President | Jean-Claude Brou |
Executive Director of the Nigerian Export Promotion Council | |
In office February 2018 – November 2021 | |
Ààrẹ | Muhammadu Buhari |
In office November 2013 – November 2017 | |
Ààrẹ | Goodluck Jonathan Muhammadu Buhari |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | Olusegun Awolowo Jr. 27 Oṣù Kẹ̀sán 1963 |
Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
Education | |
Profession | Lawyer |
Olúṣẹ́gun Awólọ́wọ̀ Jr. (wọ́n bí i ní 27 September 1963), jẹ́ agbẹjọ́rò ọmọ nàìjíríà, ó jẹ́ Alákòóso Àgbà fún Nigerian Export Promotion Council, láti ọdún 2013 dé ọdún 2021 .[1][2]. Ó jẹ́ ọmọ-ọmọ àgbà Olóṣèlù Nàìjíríà nnì, Olóyè Obafemi Awolowo .[3] Ní oṣù keje ọdún 2021, wọ́n panupọ̀ dìbò yàn-án gẹ́gẹ́ bí i ààrẹ àwọn àjọ tóń ṣe ìgbélárugẹ fún òwò ní orílẹ̀ èdè yìí (TPOs) láti ara ECOWAS member States.[4][5]
© MMXXIII Rich X Search. We shall prevail. All rights reserved. Rich X Search